Skip to content

Àwọn ẹsẹ Bíbélì nípa Shem

81 ẹsẹ · 4 abala

Àwọn ẹsẹ Bíbélì pàtàkì

Sẹ́ nípa ìwé
  1. Nígbà tí Baali-Hanani kú, Hadadi ni ó jẹ ọba ní ipò rẹ̀. Orúkọ ìlú rẹ̀ ni Pau; orúkọ ìyàwó sì ni Mehetabeeli ọmọbìnrin Matiredi, ọmọbìnrin Mesahabu.

  2. Hadadi sì kú pẹ̀lú. Àwọn baálẹ̀ Edomu ni: baálẹ̀ Timna, baálẹ̀ Alfa, baálẹ̀ Jeteti

  3. baálẹ̀ Oholibama, baálẹ̀ Ela, baálẹ̀ Pinoni.

  4. Baálẹ̀ Kenasi, baálẹ̀ Temani, baálẹ̀ Mibsari,

  5. Magdieli àti Iramu. Àwọn wọ̀nyí ni baálẹ̀ Edomu.

  6. Tí í ṣe ọmọ Kainani, tí í ṣe ọmọ Arfaksadi, tí í ṣe ọmọ Ṣemu, tí í ṣe ọmọ Noa, tí í ṣe ọmọ Lameki,