Random Bible Verse

YCB
313 nínú 31,102
Nígbà tí Abramu dé Ejibiti, àwọn ará Ejibiti ri i pé aya rẹ̀ rẹwà gidigidi.
Gẹnẹsisi 12:14
Abramu tan Fáráò jẹ ní Íjíbítì
100%
Ìṣesí Ẹsẹ Ìwé Mímọ́

Ó kan ẹsẹ rẹ tó ń bọ̀

100%
Ìrísí lẹ́tà
Ìṣesí Ẹsẹ Ìwé Mímọ́

Ó kan ẹsẹ rẹ tó ń bọ̀

I. Nínú àyíká ọ̀rọ̀ Ìpín 5,439 · Orí 1,189
Abala Yìí Gẹnẹsisi 12:10-20
10 Ìyàn kan sì mú ní ilẹ̀ náà, Abramu sì sọ̀kalẹ̀ lọ sí Ejibiti láti ṣe àtìpó níbẹ̀ fún ìgbà díẹ̀, nítorí ìyàn náà mú gidigidi.
11 Bí ó ti ku díẹ̀ kí ó wọ Ejibiti, ó wí fún Sarai, aya rẹ̀ pé, “Mo mọ̀ pé arẹwà obìnrin ni ìwọ,
+ 9 more verses · Gẹnẹsisi 12:10-20
Ṣí
Orí Yìí Gẹnẹsisi 12
1 Olúwa sì wí fún Abramu, “Jáde kúrò ní orílẹ̀-èdè rẹ àti kúrò lọ́dọ̀ àwọn ènìyàn rẹ, lọ sí ilẹ̀ kan tí èmi yóò fihàn ọ́.
2 “Èmi yóò sọ ọ́ di orílẹ̀-èdè ńlá, èmi yóò sì bùkún fún ọ; èmi yóò sọ orúkọ rẹ di ńlá, ìbùkún ni ìwọ yóò sì jásí.
3 Èmi yóò bùkún fún àwọn tí ó súre fún ọ, ẹni tí ó fi ọ́ ré ni Èmi yóò fi ré; nínú rẹ ni a ó bùkún gbogbo ìdílé ayé.”
+ 17 more · Gẹnẹsisi 12
Ṣí
III. Túnú ká Irinṣẹ́ ìkẹ́kọ̀ọ́ 4

Lẹ́yìn gbogbo ẹsẹ lórí ojú-òpó wẹ́ẹ̀bù yìí, àwọn irinṣẹ́ ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì ọ̀fẹ́ wà — Strong's, àwọn ìtọkasí ẹsẹ, àlàyé Matthew Henry, olùkọ́ AI tí ó ń tọ́ka sí iṣẹ́ rẹ̀, àwọn ìwé ìrònú, àti ìkẹ́kọ̀ọ́ jinlẹ̀ lórí àwọn kókó-ọ̀rọ̀. Má kàn ka ẹsẹ náà. Tú u wò dáadáa.

IV. Mú un dání áàpù àti àfikún