Fò sí àkóónú

Àwọn ẹsẹ Bíbélì nípa The Reward of Saints: Rest

2 ẹsẹ · 51 abala

Àwọn ẹsẹ nípa Rest

  1. nítorí náà ìsinmi kan kù fún àwọn ènìyàn Ọlọ́run.

  2. Mo sì gbọ́ ohùn kan láti ọ̀run wá ń wí fún mi pé, “Kọ̀wé rẹ̀, Alábùkún fún ni àwọn òkú tí o kú nínú Olúwa láti ìhín lọ.” Alábùkún ni wọ́n nítòótọ́, bẹ́ẹ̀ ni, Ẹ̀mí wí, “Nítorí tí wọn yóò sinmi kúrò nínú làálàá wọn, nítorí iṣẹ́ wọn ń tọ̀ wọn lẹ́yìn.”