Fò sí àkóónú

Àwọn ẹsẹ Bíbélì nípa The Reward of Saints: A kingdom

2 ẹsẹ · 51 abala

Àwọn ẹsẹ nípa A kingdom

  1. “Nígbà náà ni ọba yóò wí fún àwọn tí ó wà lọ́wọ́ ọ̀tún pé, ‘Ẹ wá, ẹ̀yin tí Baba mi ti bùkún fún, ẹ jogún ìjọba tí a ti pèsè fún yín láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ ayé.

  2. Mo sì yan ìjọba fún yín, gẹ́gẹ́ bí Baba mi ti yàn fún mi.