Fò sí àkóónú

Àwọn ẹsẹ Bíbélì nípa The Reward of Saints: Shall be given at the second coming of Christ

2 ẹsẹ · 51 abala

Àwọn ẹsẹ nípa Shall be given at the second coming of Christ

  1. Nítorí Ọmọ Ènìyàn yóò wá nínú ògo baba rẹ pẹ̀lú àwọn angẹli rẹ̀, nígbà náà ni yóò sì san án fún olúkúlùkù gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ rẹ̀.

  2. “Kíyèsi i, èmi ń bọ̀ kánkán; èrè mí sì ń bẹ pẹ̀lú mi, láti sán fún olúkúlùkù gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ rẹ̀ yóò tí rí.