Fò sí àkóónú

Àwọn ẹsẹ Bíbélì nípa Serpents: Of enemies who harass and destroy

2 ẹsẹ · 26 abala

Àwọn ẹsẹ nípa Of enemies who harass and destroy

  1. Má ṣe yọ̀, gbogbo ẹ̀yin Filistia, pé ọ̀pá tí ó lù ọ́ ti dá; láti ibi gbòǹgbò ejò náà ni paramọ́lẹ̀ yóò ti hù jáde, èso rẹ̀ yóò sì jẹ́ oró ejò tí í jóni.

  2. “Wò ó, èmi yóò rán àwọn ejò olóró sí àárín yín, paramọ́lẹ̀ tí ẹ kò lè pa oró wọn, yóò sì bù yín jẹ,” ni Olúwa wí.