Skip to content
Numeri 34:16-29

Numeri 34:16-29

16
Olúwa sọ fún Mose pé,
17
“Èyí ni orúkọ àwọn ọkùnrin náà tí yóò pín ilẹ̀, náà fún yín gẹ́gẹ́ bí ogún: Eleasari àlùfáà àti Joṣua ọmọ Nuni.
18
Kí o sì yan olórí kan nínú ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan láti pín ilẹ̀ náà.
19
“Èyí ni orúkọ wọn: “Kalebu ọmọ Jefunne, láti ẹ̀yà Juda;
20
Ṣemueli ọmọ Ammihudu, láti ẹ̀yà Simeoni;
21
Elidadi ọmọ Kisloni, láti ẹ̀yà Benjamini;
22
Bukki ọmọ Jogli, láti ẹ̀yà olórí àwọn ọmọ Dani;
23
Hannieli ọmọ Efodu, láti ẹ̀yà Manase, olórí àwọn ọmọ Josẹfu,
24
Kemueli ọmọ Ṣiftani, olórí ẹ̀yà àwọn ọmọ, Efraimu, ọmọ Josẹfu;
25
Elisafani ọmọ Parnaki, olórí ẹ̀yà àwọn ọmọ Sebuluni;
26
Paltieli ọmọ Assani, olórí ẹ̀yà àwọn ọmọ Isakari;
27
Ahihudu ọmọ Ṣelomi, olórí ẹ̀yà àwọn ọmọ Aṣeri;
28
Pedaheli ọmọ Ammihudu, olórí ẹ̀yà àwọn ọmọ Naftali.”
29
Èyí ni àwọn ẹni tí Olúwa yàn láti pín ogún náà fún àwọn ọmọ Israẹli ní ilẹ̀ Kenaani.
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Options