Fò sí àkóónú

Àwọn ẹsẹ Bíbélì nípa Woman: From one of Adam's ribs

2 ẹsẹ · 73 abala

Àwọn ẹsẹ nípa From one of Adam's ribs

  1. Nígbà náà ni Olúwa Ọlọ́run mú kí ọkùnrin náà sùn fọnfọn; nígbà tí ó sì ń sùn, Ọlọ́run yọ egungun ìhà rẹ̀ kan, ó sì fi ẹran-ara bò ó padà.

  2. Olúwa Ọlọ́run sì dá obìnrin láti inú egungun tí ó yọ ní ìhà ọkùnrin náà, Ó sì mu obìnrin náà tọ̀ ọ́ wá.