Nehemiah 11:25-36
25
Fún ìletò pẹ̀lú oko wọn, díẹ̀ nínú àwọn ènìyàn Juda tí ń gbé Kiriati-Arba, àti àwọn ìletò agbègbè e rẹ̀, ní Diboni àti ìletò rẹ̀, ní Jekabseeli.
26
Ní Jeṣua, ní Molada, ní Beti-Peleti
27
ní Hasari-Ṣuali, ní Beerṣeba àti àwọn agbègbè rẹ̀.
28
Ní Siklagi, ní Mekona àti àwọn ìletò rẹ̀,
29
ní Ẹni-Rimoni, ní Sora, ní Jarmatu,
30
Sanoa, Adullamu àti àwọn ìletò o wọn, ní Lakiṣi àti àwọn oko rẹ̀, àti ní Aseka àti àwọn ìletò rẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ń gbé láti Beerṣeba títí dé àfonífojì Hinnomu.
31
Àwọn ọmọ Benjamini láti Geba ń gbé ní Mikmasi, Aija, Beteli àti àwọn ìletò rẹ̀.
32
Ní Anatoti, Nobu àti Ananiah,
33
ní Hasori Rama àti Gittaimu,
34
ní Hadidi, Seboimu àti Neballati,
35
ní Lodi àti Ono, àti ní àfonífojì àwọn gbẹ́nàgbẹ́nà.
36
Nínú ìpín àwọn ọmọ Lefi ni Juda tẹ̀dó sí Benjamini.
Settings