Nehemiah 11:25-30
25
Fún ìletò pẹ̀lú oko wọn, díẹ̀ nínú àwọn ènìyàn Juda tí ń gbé Kiriati-Arba, àti àwọn ìletò agbègbè e rẹ̀, ní Diboni àti ìletò rẹ̀, ní Jekabseeli.
26
Ní Jeṣua, ní Molada, ní Beti-Peleti
27
ní Hasari-Ṣuali, ní Beerṣeba àti àwọn agbègbè rẹ̀.
28
Ní Siklagi, ní Mekona àti àwọn ìletò rẹ̀,
29
ní Ẹni-Rimoni, ní Sora, ní Jarmatu,
30
Sanoa, Adullamu àti àwọn ìletò o wọn, ní Lakiṣi àti àwọn oko rẹ̀, àti ní Aseka àti àwọn ìletò rẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ń gbé láti Beerṣeba títí dé àfonífojì Hinnomu.
Settings