Skip to content

Àwọn ẹsẹ Bíbélì nípa Micah

12 ẹsẹ · 5 abala

Àwọn ẹsẹ Bíbélì pàtàkì

  1. Mefiboṣeti sì ní ọmọ kékeré kan, orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Mika. Gbogbo àwọn tí ń gbé ní ilé Ṣiba ni ó sì ń ṣe ìránṣẹ́ fún Mefiboṣeti.

  2. Mika ọmọ rẹ̀, Reaiah ọmọ rẹ̀, Baali ọmọ rẹ̀.

  3. Ọmọ Jonatani: Meribu-Baali tí ó jẹ́ baba Mika.

  4. Àwọn ọmọ Mika: Pitoni, Meleki, Tarea, àti Ahasi.

  5. Ọmọ Jonatani: Meribu-Baali, tí ó jẹ́ baba Mika.

  6. Àwọn ọmọ Mika: Pitoni. Meleki, Tarea àti Ahasi.

  7. Àwọn ọmọ Usieli: Mika ni àkọ́kọ́ àti Iṣiah ẹ̀ẹ̀kejì.

  8. Àwọn ọmọ Usieli: Mika; nínú àwọn ọmọ Mika: Ṣamiri.

  9. Àwọn arákùnrin Mika: Iṣi; nínú àwọn ọmọ Iṣiah: Sekariah.

  10. Ó sì pa àṣẹ yìí fún Hilkiah, Ahikamu ọmọ Ṣafani, Abdoni ọmọ Mika, Ṣafani akọ̀wé àti Asaiah ìránṣẹ́ ọba.

  11. Ṣùgbọ́n ẹ̀yin olùfẹ́, ẹ rántí àwọn ọ̀rọ̀ tí a ti sọ ṣáájú láti ọwọ́ àwọn aposteli Olúwa wa Jesu Kristi.

  12. Bí wọn ti wí fún yín pé, “Nígbà ìkẹyìn àwọn ẹlẹ́gàn yóò wà, tí wọn yóò máa rìn gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ àìwà-bí-Ọlọ́run ti ara wọn.”