Fò sí àkóónú

Micah

8 ẹsẹ · 5 ọmọ ẹbí

A tún mọ̀ ọ́n sí: Micha

Àwọn ẹsẹ tí ó mẹ́nu kan Micah

  1. Nígbà tí àwọn ọkùnrin yìí wọ ilé e Mika lọ tí wọ́n sì kó ère fínfín náà, efodu náà, àwọn òrìṣà ìdílé mìíràn àti ère dídà náà, àlùfáà náà béèrè lọ́wọ́ wọn wí pé, “Kí ni ẹ̀yin ń ṣe?”

  2. Nígbà tí wọ́n ti rìn jìnnà díẹ̀ sí ilé Mika, àwọn ọkùnrin tí ó wà ní agbègbè Mika kó ara wọn jọ, wọ́n sì lé àwọn ará Dani bá.

  3. Wọ́n tẹ̀síwájú láti lo àwọn ère tí Mika ṣe, ní gbogbo àkókò tí ilé Ọlọ́run wà ní Ṣilo.

  4. Mefiboṣeti sì ní ọmọ kékeré kan, orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Mika. Gbogbo àwọn tí ń gbé ní ilé Ṣiba ni ó sì ń ṣe ìránṣẹ́ fún Mefiboṣeti.

  5. Ọmọ Jonatani: Meribu-Baali tí ó jẹ́ baba Mika.

  6. Àwọn ọmọ Mika: Pitoni, Meleki, Tarea, àti Ahasi.

  7. Ọmọ Jonatani: Meribu-Baali, tí ó jẹ́ baba Mika.

  8. Àwọn ọmọ Mika: Pitoni. Meleki, Tarea àti Ahasi.