Fò sí àkóónú

Àwọn ẹsẹ Bíbélì nípa Union With Christ: Have, in sufferings

2 ẹsẹ · 41 abala

Àwọn ẹsẹ nípa Have, in sufferings

  1. Èmi mọ̀ ọ́n, àti agbára àjíǹde rẹ̀, àti láti jẹ́ alábápín nínú ìyà rẹ̀ nígbà tí mo bá fi ara mọ́ ọn nínú ikú rẹ̀;

  2. Bí àwa bá faradà, àwa ó sì bá a jẹ ọba. Bí àwa bá sẹ́ ẹ, òun náà yóò sì sẹ́ wa.