Fò sí àkóónú

Àwọn ẹsẹ Bíbélì nípa Medes: Supremacy of, in the Chaldean empire

4 ẹsẹ · 4 abala

Àwọn ẹsẹ nípa Supremacy of, in the Chaldean empire

  1. “Peresini: A ti pín ìjọba rẹ a sì ti fi fún àwọn Media àti àwọn Persia.”

  2. Dariusi ará Media sì gba ìjọba nígbà tí ó di ọmọ ọdún méjìlélọ́gọ́ta.

  3. Ní ọdún kìn-ín-ní Dariusi ọmọ Ahaswerusi, ẹni tí a bí ní Media, òun ló jẹ ọba lórí ìjọba Babeli.

  4. Ní ọdún kìn-ín-ní Dariusi ará Media, mo dúró láti tì í lẹ́yìn àti láti dáàbò bò ó.)