Fò sí àkóónú

Àwọn ẹsẹ Bíbélì nípa Children: Prosperity of, greatly depended on obedience of parents

3 ẹsẹ · 102 abala

Àwọn ẹsẹ nípa Prosperity of, greatly depended on obedience of parents

  1. Orin fún ìgòkè. Ìbùkún ni fún gbogbo ẹni tí ó bẹ̀rù Olúwa: tí ó sì ń rìn ní ọ̀nà rẹ̀.

  2. Nítorí tí ìwọ yóò jẹ iṣẹ́ ọwọ́ rẹ ìbùkún ni fún ọ; yóò sì dára fún ọ.

  3. Obìnrin rẹ yóò dàbí àjàrà rere eléso púpọ̀ ní àárín ilé rẹ; àwọn ọmọ rẹ yóò dàbí igi olifi tí ó yí tábìlì rẹ ká.