Fò sí àkóónú
Saamu 58:10-11

Ìdáláre ìdájọ́ òdodo Ọlọ́run

Saamu 58:10-11
10
Olódodo yóò yọ̀ nígbà a bá ń gbẹ̀san wọn, nígbà tí wọn bá wẹ ẹsẹ̀ wọn nínú ẹ̀jẹ̀ ènìyàn búburú.
11
Àwọn ènìyàn yóò wí pé, “Lóòtítọ́ èrè àwọn ń bẹ fún olódodo; lóòtítọ́ òun ni Ọlọ́run tí ń ṣe ìdájọ́ ní ayé.”
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Reading Width 45 chars

Options