Fò sí àkóónú
Onidajọ 10:17-18

Ìmúrasílẹ̀ fún ogun sí Amoni

Onidajọ 10:17-18
17
Nígbà tí àwọn ará Ammoni kógun jọ ní Gileadi láti bá Israẹli jà, àwọn ọmọ Israẹli gbárajọpọ̀, wọ́n sì tẹ̀dó ogun ní Mispa.
18
Àwọn ìjòyè: aṣíwájú àwọn ará Gileadi wí fún ará wọn pé, “Ẹnikẹ́ni tí yóò kọ́ ṣígun si àwọn ará Ammoni ni yóò jẹ́ orí fún gbogbo àwọn tí ń gbé ní Gileadi.”
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Reading Width 45 chars

Options