Fò sí àkóónú
Gẹnẹsisi 20:17-18

Abrahamu bẹ̀bẹ̀ fún Abimeleki

Gẹnẹsisi 20:17-18
17
Nígbà náà, Abrahamu gbàdúrà sí Ọlọ́run, Ọlọ́run sì wo Abimeleki àti aya rẹ̀ àti àwọn ẹrúbìnrin rẹ̀ sàn. Wọ́n sì tún ń bímọ,
18
nítorí Olúwa ti sé gbogbo ará ilé Abimeleki nínú nítorí Sara aya Abrahamu.
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Reading Width 45 chars

Options