Fò sí àkóónú

Àwọn ẹsẹ Bíbélì nípa The Anger of God: Manifested in judgments and afflictions

3 ẹsẹ · 43 abala

Àwọn ẹsẹ nípa Manifested in judgments and afflictions

  1. Ó mú kíkorò ìbínú rẹ̀ wá sí wọn lára, ìrunú àti ìkáàánú, àti ìpọ́njú, nípa rírán angẹli apanirun sí wọn.

  2. Ó pèsè ipa fún ìbínú rẹ̀, òun kò gbà wọ́n lọ́wọ́ ikú, ṣùgbọ́n ó fi ẹ̀mí wọ́n fún àjàkálẹ̀-ààrùn.

  3. Ó kọlu àwọn àkọ́bí ọmọ ọkùnrin Ejibiti, olórí agbára wọn nínú àgọ́ Hamu.