Skip to content

Àwọn ẹsẹ Bíbélì nípa Nimrod

3 ẹsẹ · 1 abala

Àwọn ẹsẹ Bíbélì pàtàkì

  1. Kuṣi sì bí Nimrodu, ẹni tí ó di alágbára jagunjagun ní ayé.

  2. Ó sì jẹ́ ògbójú ọdẹ níwájú Olúwa; nítorí náà ni a ṣe ń wí pé, “Bí Nimrodu, ògbójú ọdẹ níwájú Olúwa.”

  3. Kuṣi sì bí Nimrodu ẹni tí ó di alágbára jagunjagun ní ayé.