Fò sí àkóónú

Àwọn ẹsẹ Bíbélì nípa Christ is God: As Lord of all

3 ẹsẹ · 55 abala

Àwọn ẹsẹ nípa As Lord of all

  1. Nítorí Ìwé Mímọ́ wí pé, “Ẹnikẹ́ni tí ó bá gbà a gbọ́ ojú kò yóò tì í.”

  2. Nítorí kò si ìyàtọ̀ nínú Júù àti Helleni: nítorí Olúwa kan náà ni Olúwa gbogbo wọn, o si pọ̀ ni ọrọ̀ fún gbogbo àwọn ti ń ké pe e.

  3. “Ẹnikẹ́ni tí ó bá sá à ti pe orúkọ Olúwa ni a ó gbàlà.”