Fò sí àkóónú
Gẹnẹsisi 48:21-22

Àsọtẹ́lẹ̀ ìkẹyìn Jákọ́bù àti ẹ̀bùn rẹ̀

Gẹnẹsisi 48:21-22
21
Nígbà náà ni Israẹli wí fún Josẹfu pé, “Ọjọ́ ikú mi súnmọ́ etílé, ṣùgbọ́n Ọlọ́run yóò wà pẹ̀lú yín, yóò sì mú un yín padà sí ilẹ̀ àwọn baba yín.
22
Pẹ̀lúpẹ̀lú èmi yóò fún ọ ní ìpín kan ju ti àwọn arákùnrin rẹ lọ. Ilẹ̀ tí mo fi idà àti ọ̀kọ̀ mi gbà lọ́wọ́ àwọn ará Amori.”
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Reading Width 45 chars

Options