1 Kronika 8:6-27
6
Wọ̀nyí ni àwọn ìran ọmọ Ehudu, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé tí ó ń gbé ní Geba tí a sì lé kúrò lọ sí Manahati:
7
Naamani Ahijah àti Gera, tí ó lé wọn kúrò ní ìlú, àti tí ó sì jẹ́ baba Ussa àti Ahihudu.
8
A bí àwọn ọmọkùnrin fún Ṣaharaimu ní Moabu lẹ́yìn tí ó ti kọ àwọn ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀, Huṣimu àti Baara.
9
Nípasẹ̀ ìyàwó rẹ̀ Hodeṣi ó ní Jobabu Sibia, Meṣa, Malkamu,
10
Jeusi, Sakia àti Mirma. Wọ̀nyí ni àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, olórí àwọn ìdílé.
11
Nípasẹ̀ Huṣimu ó ní Abitubu àti Elipali.
12
Àwọn ọmọ Elipali: Eberi, Miṣamu, Ṣemedu (ẹni tí ó kọ́ Ono àti Lodi pẹ̀lú àwọn ìletò àyíká rẹ̀.)
13
Pẹ̀lú Beriah àti Ṣema, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé ti àwọn tí ó ń gbé ní Aijaloni àti àwọn tí ó lé àwọn olùgbé Gati kúrò.
14
Ahio, Ṣasaki, Jeremoti,
15
Sebadiah, Aradi, Ederi
16
Mikaeli, Iṣifa àti Joha jẹ́ àwọn ọmọ Beriah.
17
Sebadiah, Meṣullamu, Hiski, Heberi
18
Iṣimerai, Isiliahi àti Jobabu jẹ́ àwọn ọmọ Elipali.
19
Jakimu, Sikri, Sabdi,
20
Elienai, Siletai, Elieli,
21
Adaiah, Beraiah àti Ṣimrati jẹ́ àwọn ọmọ, Ṣimei.
22
Iṣipani Eberi, Elieli,
23
Abdoni, Sikri, Hanani,
24
Hananiah, Elamu, Anitotijah,
25
Ifediah àti Penueli jẹ́ àwọn ọmọ Ṣasaki.
26
Ṣamṣerai, Ṣeharaiah, Ataliah
27
Jareṣiah, Elijah àti Sikri jẹ́ àwọn ọmọ Jerohamu.
Settings