Fò sí àkóónú
Saamu 32:6-7

Ààbò àti ìgbàlà nínú Ọlọ́run

Saamu 32:6-7
6
Nítorí náà jẹ́ kí gbogbo àwọn olódodo máa gbà àdúrà sí ọ ní ìgbà tí a lè rí ọ; nítòótọ́ nígbà tí ìṣàn omi ńlá bá ru sókè, wọn kì yóò lè dé ọ̀dọ̀ rẹ̀.
7
Ìwọ ni ibi ìpamọ́ mi; ìwọ yóò pa mí mọ́ kúrò nínú ìyọnu; ìwọ yóò fi orin ìgbàlà yí mi ka. Sela.
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Reading Width 45 chars

Options