Fò sí àkóónú
Numeri 30:1-2

Ìṣáájú sí òfin ẹ̀jẹ́

Numeri 30:1-2
1
Mose sì sọ fún olórí àwọn ẹ̀yà ọmọ Israẹli pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa pàṣẹ,
2
nígbà tí ọkùnrin kan bá jẹ́ ẹ̀jẹ́ sí Olúwa tàbí búra láti fi de ara rẹ̀ ní ìdè kí òun má bà ba ọ̀rọ̀ rẹ̀ jẹ́ kí ó ṣe gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe sọ.
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Reading Width 45 chars

Options