Fò sí àkóónú
Nehemiah 10:1-29

Nehemiah 10:1-29

1
Àwọn tí ó fi èdìdì dì í ni: Nehemiah baálẹ̀, ọmọ Hakaliah. Sedekiah
2
Seraiah, Asariah, Jeremiah,
3
Paṣuri, Amariah, Malkiah,
4
Hattusi, Ṣebaniah, Malluki,
5
Harimu, Meremoti, Obadiah,
6
Daniẹli, Ginetoni, Baruku,
7
Meṣullamu, Abijah, Mijamini,
8
Maasiah, Bilgai àti Ṣemaiah. Àwọn wọ̀nyí ni àwọn àlùfáà.
9
Àwọn ọmọ Lefi: Jeṣua ọmọ Asaniah, Binnui ọ̀kan nínú àwọn ọmọ Henadadi, Kadmieli,
10
àti àwọn ẹlẹgbẹ́ ẹ wọn: Ṣebaniah, Hodiah, Kelita, Pelaiah, Hanani,
11
Mika, Rehobu, Haṣabiah,
12
Sakkuri, Ṣerebiah, Ṣebaniah,
13
Hodiah, Bani àti Beninu.
14
Àwọn olórí àwọn ènìyàn: Paroṣi, Pahati-Moabu, Elamu, Sattu, Bani,
15
Bunni, Asgadi, Bebai.
16
Adonijah, Bigfai, Adini,
17
Ateri, Hesekiah, Assuri,
18
Hodiah, Haṣumu, Besai,
19
Harifu, Anatoti, Nebai,
20
Magpiaṣi, Meṣullamu, Hesiri
21
Meṣesabeli, Sadoku, Jaddua
22
Pelatiah, Hanani, Anaiah,
23
Hosea, Hananiah, Haṣubu,
24
Halloheṣi, Pileha, Ṣobeki,
25
Rehumu, Haṣabna, Maaseiah,
26
Ahijah, Hanani, Anani,
27
Malluki, Harimu, àti Baanah.
28
“Àwọn ènìyàn tókù—àwọn àlùfáà, àwọn ọmọ Lefi, àwọn aṣọ́nà, àwọn ìránṣẹ́ tẹmpili àti gbogbo àwọn tí wọ́n ya ara wọn sọ́tọ̀ kúrò lára àwọn ènìyàn àjèjì nítorí òfin Ọlọ́run, papọ̀ pẹ̀lú ìyàwó wọn, gbogbo ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin wọn, tí òye yé
29
gbogbo wọn fi ara mọ́ àwọn arákùnrin wọn, àwọn ọlọ́lá, wọ́n sì fi ègún àti ìbúra dé ara wọn láti máa tẹ̀lé òfin Ọlọ́run tí a fi fún wọn ní ipasẹ̀ Mose ìránṣẹ́ Ọlọ́run àti láti pa gbogbo àṣẹ, ìlànà àti òfin Olúwa, wa mọ́ dáradára.
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Reading Width 45 chars

Options