Nehemiah 10:1-27
1
Àwọn tí ó fi èdìdì dì í ni: Nehemiah baálẹ̀, ọmọ Hakaliah. Sedekiah
2
Seraiah, Asariah, Jeremiah,
3
Paṣuri, Amariah, Malkiah,
4
Hattusi, Ṣebaniah, Malluki,
5
Harimu, Meremoti, Obadiah,
6
Daniẹli, Ginetoni, Baruku,
7
Meṣullamu, Abijah, Mijamini,
8
Maasiah, Bilgai àti Ṣemaiah. Àwọn wọ̀nyí ni àwọn àlùfáà.
9
Àwọn ọmọ Lefi: Jeṣua ọmọ Asaniah, Binnui ọ̀kan nínú àwọn ọmọ Henadadi, Kadmieli,
10
àti àwọn ẹlẹgbẹ́ ẹ wọn: Ṣebaniah, Hodiah, Kelita, Pelaiah, Hanani,
11
Mika, Rehobu, Haṣabiah,
12
Sakkuri, Ṣerebiah, Ṣebaniah,
13
Hodiah, Bani àti Beninu.
14
Àwọn olórí àwọn ènìyàn: Paroṣi, Pahati-Moabu, Elamu, Sattu, Bani,
15
Bunni, Asgadi, Bebai.
16
Adonijah, Bigfai, Adini,
17
Ateri, Hesekiah, Assuri,
18
Hodiah, Haṣumu, Besai,
19
Harifu, Anatoti, Nebai,
20
Magpiaṣi, Meṣullamu, Hesiri
21
Meṣesabeli, Sadoku, Jaddua
22
Pelatiah, Hanani, Anaiah,
23
Hosea, Hananiah, Haṣubu,
24
Halloheṣi, Pileha, Ṣobeki,
25
Rehumu, Haṣabna, Maaseiah,
26
Ahijah, Hanani, Anani,
27
Malluki, Harimu, àti Baanah.
Settings