Fò sí àkóónú
Gẹnẹsisi 23:3-6

Abrahamu béèrè ibi ìsìnkú

Gẹnẹsisi 23:3-6
3
Abrahamu sì dìde lẹ́gbẹ̀ẹ́ òkú aya rẹ̀, ó sì sọ fún àwọn ará Hiti wí pé,
4
“Èmi jẹ́ àtìpó àti àlejò láàrín yín, ẹ ta ilẹ̀ ìsìnkú fún mi kí èmi le sin òkú tí ó kú fún mi sí.”
5
Àwọn ọmọ Hiti dá Abrahamu lóhùn pé,
6
“Olúwa mi, gbọ́ tiwa, ó jẹ́ alágbára ọmọ-aládé láàrín wa, sin òkú rẹ sí ibojì tí ó dára jù nínú àwọn ibojì wa, kò sí ẹni tí yóò fi ibojì rẹ dù ọ́ láti sin òkú rẹ sí.”
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Reading Width 45 chars

Options