Fò sí àkóónú

Àwọn ẹsẹ Bíbélì nípa Rogelim: The home of Barzillai.

2 ẹsẹ · 1 abala

Àwọn ẹsẹ nípa The home of Barzillai.

  1. Nígbà tí Dafidi sì wá sí Mahanaimu, Ṣobi ọmọ Nahaṣi ti Rabba tí àwọn ọmọ Ammoni, àti Makiri ọmọ Ammieli ti Lo-Debari, àti Barsillai ará Gileadi ti Rogelimu.

  2. Barsillai ará Gileadi sì sọ̀kalẹ̀ láti Rogelimu wá, ó sì bá ọba gòkè odò Jordani, láti ṣe ìkẹ́ rẹ̀ sí ìkọjá odò Jordani.