Fò sí àkóónú

Àwọn ẹsẹ Bíbélì nípa Hatred to Christ: No escape for those who persevere in

3 ẹsẹ · 10 abala

Àwọn ẹsẹ nípa No escape for those who persevere in

  1. Mélòó mélòó ni ẹ rò pé a o jẹ ẹni náà ní ìyà kíkan, ẹni tí o tẹ Ọmọ Ọlọ́run mọ́lẹ̀ tí ó sì ti ka ẹ̀jẹ̀ májẹ̀mú ti a fi sọ ọ́ di mímọ́ si ohun àìmọ́, tí ó sì ti kẹ́gàn ẹ̀mí oore-ọ̀fẹ́.

  2. Nítorí àwa mọ ẹni tí o wí pé, Ẹ̀san ni ti èmi, Olúwa wí pé, “Èmi ó gbẹ̀san.” Àti pẹ̀lú, “Olúwa yóò ṣe ìdájọ́ àwọn ènìyàn rẹ̀.”

  3. Ohun ẹ̀rù ni láti ṣubú sí ọwọ́ Ọlọ́run alààyè.