Fò sí àkóónú

Àwọn ẹsẹ Bíbélì nípa Hannah: Visits Samuel at the temple from year to year

2 ẹsẹ · 5 abala

Àwọn ẹsẹ nípa Visits Samuel at the temple from year to year

  1. Ṣùgbọ́n Samuẹli ń ṣe ìránṣẹ́ níwájú Olúwa, ọmọdé, ti a wọ̀ ní efodu ọ̀gbọ̀.

  2. Pẹ̀lúpẹ̀lú, ìyá rẹ̀ máa ń dá aṣọ ìlekè péńpé fún un, a sì máa mú wá fún un lọ́dọọdún, nígbà tí ó bá bá ọkọ rẹ̀ gòkè wá láti ṣe ìrúbọ ọdún.