Fò sí àkóónú
Saamu 2:4-6

OLÚWA ń rẹ́rìn-ín sí ètò wọn

Saamu 2:4-6
4
Ẹni tí ó gúnwà lórí ìtẹ́ lọ́run rẹ́rìn-ín; Olúwa fi wọ́n rẹ́rìn-ín ẹlẹ́yà.
5
Nígbà náà ni yóò bá wọn wí ní ìbínú rẹ̀ yóò sì dẹ́rùbà wọ́n ní ìrunú rẹ̀, ó wí pé,
6
“Èmi ti fi ọba mi sí ipò lórí Sioni, òkè mímọ́ mi.”
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Reading Width 45 chars

Options