Numeri 13:3-16
3
Mose sì rán wọn jáde láti aginjù Parani gẹ́gẹ́ bí àṣẹ Olúwa. Gbogbo wọn jẹ́ olórí àwọn ènìyàn Israẹli.
4
Orúkọ wọn nìwọ̀nyí: láti inú ẹ̀yà Reubeni, Ṣammua ọmọ Sakkuri;
5
láti inú ẹ̀yà Simeoni, Ṣafati ọmọ Hori;
6
láti inú ẹ̀yà Juda, Kalebu ọmọ Jefunne;
7
láti inú ẹ̀yà Isakari, Igali ọmọ Josẹfu;
8
láti inú ẹ̀yà Efraimu, Hosea ọmọ Nuni;
9
láti inú ẹ̀yà Benjamini, Palti ọmọ Rafu;
10
láti inú ẹ̀yà Sebuluni, Daddieli ọmọ Sodi;
11
láti inú ẹ̀yà Manase (ẹ̀yà Josẹfu), Gaddi ọmọ Susi;
12
láti inú ẹ̀yà Dani, Ammieli ọmọ Gemalli;
13
láti inú ẹ̀yà Aṣeri, Seturu ọmọ Mikaeli.
14
láti inú ẹ̀yà Naftali, Nabi ọmọ Fofsi;
15
láti inú ẹ̀yà Gadi, Geueli ọmọ Maki.
16
Wọ̀nyí ni orúkọ àwọn ènìyàn tí Mose rán láti lọ yẹ ilẹ̀ náà wò. (Hosea ọmọ Nuni ni Mose sọ ní Joṣua.)
Settings