Fò sí àkóónú
Eksodu 22:21-24

Ìdájọ́ fún àwọn aláìlera

Eksodu 22:21-24
21
“Ẹ má ṣe fi ìyà jẹ àlejò tàbí ni wọ́n lára, nítorí ìwọ pẹ̀lú ti jẹ́ àjèjì ni ilẹ̀ Ejibiti rí.
22
“Má ṣe yan opó tàbí ọmọ òrukàn jẹ.
23
Bí ìwọ bá ṣe bẹ́ẹ̀, bí wọn bá ké pè mi. Èmi yóò sì gbọ́ ohùn igbe wọn.
24
Ìbínú mi yóò ru sókè. Èmi yóò sì fi idà pa ọ. Ìyàwó rẹ yóò di opó, àwọn ọmọ rẹ yóò sì di aláìní baba.
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Reading Width 45 chars

Options