Fò sí àkóónú
Daniẹli 8:1-2

Ìran Ní Ṣúṣánì

Daniẹli 8:1-2
1
Nígbà tí ó di ọdún kẹta ìjọba Belṣassari ọba, èmi Daniẹli rí ìran kan èyí tí mo ti rí tẹ́lẹ̀.
2
Nínú ìran náà, mo rí ara mi nínú ilé ìṣọ́ ní Susa ní agbègbè ìjọba Elamu: nínú ìran náà mo wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ odò Ulai.
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Reading Width 45 chars

Options