Fò sí àkóónú
Sekariah 1:20-21

Sekariah 1:20-21

20
Olúwa sì fi alágbẹ̀dẹ mẹ́rin kan hàn mí.
21
Nígbà náà ni mo wí pé, “Kí ni àwọn wọ̀nyí wá ṣe?” O sì sọ wí pé, “Àwọn wọ̀nyí ni ìwo tí ó ti tú Juda ká, tó bẹ́ẹ̀ tí ẹnikẹ́ni kò fi gbé orí rẹ̀ sókè? Ṣùgbọ́n àwọn wọ̀nyí wá láti dẹ́rùbà wọ́n, láti lé ìwo àwọn orílẹ̀-èdè jáde, ti wọ́n gbé ìwo wọn sórí ilẹ̀ Juda láti tú ènìyàn rẹ̀ ká.”
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Reading Width 45 chars

Options