Fò sí àkóónú
Saamu 95:8-9

Saamu 95:8-9

8
“Ẹ má ṣe sé ọkàn yín le gẹ́gẹ́ bí ẹ ti ṣe ní Meriba, àti bí ẹ ti ṣe ní ọjọ́ náà ní Massa ní aginjù,
9
nígbà tí àwọn baba yín dán mi wò tí wọn wádìí mi, tí wọn sì rí iṣẹ́ mi.
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Reading Width 45 chars

Options