Fò sí àkóónú
Saamu 12:5-6

Ìlérí OLÚWA láti ṣiṣẹ́

Saamu 12:5-6
5
“Nítorí ìnilára àwọn aláìlágbára àti ìkérora àwọn aláìní, Èmi yóò dìde nísinsin yìí,” ni Olúwa wí. “Èmi yóò dáàbò bò wọ́n lọ́wọ́ àwọn tí ń ṣe àrankàn wọn.”
6
Ọ̀rọ̀ Olúwa sì jẹ aláìlábùkù, gẹ́gẹ́ bí fàdákà tí a yọ́ nínú ìléru amọ̀, tí a sọ di mímọ́ nígbà méje.
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Reading Width 45 chars

Options