Luku 9:53-56
53
Wọn kò sì gbà á, nítorí pé ó ń lọ sí Jerusalẹmu.
54
Nígbà tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ Jakọbu àti Johanu sì rí i, wọ́n ní, “Olúwa wa, jẹ́ kí a pe iná láti ọ̀run wá, kí a sì pa wọ́n run, bí Elijah ti ṣe?”
55
Ṣùgbọ́n Jesu yípadà, ó sì bá wọn wí.
56
Lẹ́yìn náà Jesu àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sì lọ sí ìletò mìíràn.
Settings