Àwọn ẹsẹ Bíbélì nípa Duty Toward The Afflicted: To visit them
Àwọn ẹsẹ nípa To visit them
Ìsìn mímọ́ àti aláìléèérí níwájú Ọlọ́run àti Baba ni èyí, láti máa bojútó àwọn aláìní baba àti àwọn opó nínú ìpọ́njú wọn, àti láti pa ara rẹ̀ mọ́ láìlábàwọ́n kúrò nínú ayé.