Saamu 136:19-22
19
Sihoni, ọba àwọn ará Amori nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.
20
Àti Ogu, ọba Baṣani; nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.
21
Ó sì fi ilẹ̀ wọn fún ni ní ìní, nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.
22
Ìní fún Israẹli, ìránṣẹ́ rẹ̀, nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.