Skip to content
Saamu 136:16-22

Saamu 136:16-22

16
Fún ẹni tí ó sin àwọn ènìyàn rẹ̀ la aginjù já nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.
17
Fún ẹni tí ó kọlu àwọn ọba ńlá; nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.
18
Ó sì pa àwọn ọba olókìkí nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.
19
Sihoni, ọba àwọn ará Amori nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.
20
Àti Ogu, ọba Baṣani; nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.
21
Ó sì fi ilẹ̀ wọn fún ni ní ìní, nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.
22
Ìní fún Israẹli, ìránṣẹ́ rẹ̀, nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Options