Saamu 136:16-22
16
Fún ẹni tí ó sin àwọn ènìyàn rẹ̀ la aginjù já nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.
17
Fún ẹni tí ó kọlu àwọn ọba ńlá; nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.
18
Ó sì pa àwọn ọba olókìkí nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.
19
Sihoni, ọba àwọn ará Amori nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.
20
Àti Ogu, ọba Baṣani; nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.
21
Ó sì fi ilẹ̀ wọn fún ni ní ìní, nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.
22
Ìní fún Israẹli, ìránṣẹ́ rẹ̀, nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.
Settings