Skip to content
Saamu 136:19-21

Saamu 136:19-21

19
Sihoni, ọba àwọn ará Amori nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.
20
Àti Ogu, ọba Baṣani; nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.
21
Ó sì fi ilẹ̀ wọn fún ni ní ìní, nítorí tí àánú rẹ̀ dúró láéláé.
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Options