Skip to content
Saamu 129:1-4

Saamu 129:1-4

1
Orin fún ìgòkè. “Ìgbà púpọ̀ ni wọ́n ti pọ́n mi lójú láti ìgbà èwe mi wá,” jẹ́ kí Israẹli kí ó wí nísinsin yìí;
2
“Ìgbà púpọ̀ ni wọ́n ti pọ́n mi lójú láti ìgbà èwe mi wá; síbẹ̀ wọn kò tí ì borí mi.
3
Àwọn awalẹ̀ walẹ̀ sí ẹ̀yìn mi: wọ́n sì la aporo wọn gígùn.
4
Olódodo ni Olúwa: ó ti ké okùn àwọn ènìyàn búburú kúrò.”
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Options