Skip to content
Saamu 126:2-3

Saamu 126:2-3

2
Nígbà náà ni ẹnu wa kún fún ẹ̀rín, àti ahọ́n wa kọ orin; nígbà náà ni wọ́n wí nínú àwọn kèfèrí pé, Olúwa ṣe ohun ńlá fún wọn.
3
Olúwa ṣe ohun ńlá fún wa; nítorí náà àwa ń yọ̀.
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Options