Saamu 114:1-5
1
Nígbà tí Israẹli jáde ní Ejibiti, ilé Jakọbu láti inú ènìyàn àjèjì èdè
2
Juda wà ní ibi mímọ́, Israẹli wà ní ìjọba.
3
Òkun sì rí i, ó sì wárìrì: Jordani sì padà sẹ́yìn.
4
Àwọn òkè ńlá ń fò bí àgbò àti òkè kéékèèké bí ọ̀dọ́-àgùntàn.
5
Kí ni ó ṣe ọ́, ìwọ Òkun, tí ìwọ fi wárìrì? Ìwọ Jordani, tí ìwọ fi padà sẹ́yìn?
Settings