Skip to content
Numeri 23:27-30

Ìmúrasílẹ̀ fún àsọtẹ́lẹ̀ kẹta

Numeri 23:27-30
27
Nígbà náà Balaki sọ fún Balaamu pé, “Wá jẹ́ kí èmi kí ó mú ọ lọ sí ibòmíràn bóyá yóò tẹ́ Ọlọ́run lọ́rùn kí ó fi wọ́n bú láti ibẹ̀ lọ.”
28
Balaki gbé Balaamu wá sí orí òkè Peori, tí ó kọjú sí aginjù.
29
Balaamu sì wí fún Balaki pé, “Mọ pẹpẹ méje fún mi níbí kí o sì pèsè akọ màlúù àti àgbò fún mi.”
30
Balaki sì ṣe bí Balaamu ti sọ fún un, ó sì gbé akọ màlúù kan àti àgbò lórí pẹpẹ kọ̀ọ̀kan.
Settings

Reading style

Typeface

Font size 19px

Reading width 90 chars

Options