Skip to content
Nehemiah 12:1-9

Nehemiah 12:1-9

1
Àwọn wọ̀nyí ni àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi tí ó bá Serubbabeli ọmọ Ṣealitieli àti Jeṣua padà: Seraiah, Jeremiah, Esra,
2
Amariah, Malluki, Hattusi,
3
Ṣekaniah, Rehumu, Meremoti,
4
Iddo, Ginetoni, Abijah,
5
Mijamini, Moadiah, Bilgah,
6
Ṣemaiah, Joiaribu, Jedaiah,
7
Sallu, Amoki, Hilkiah, àti Jedaiah. Wọ̀nyí ni olórí àwọn àlùfáà àti àwọn ẹlẹgbẹ́ ẹ wọn ní ìgbà ayé e Jeṣua.
8
Àwọn ọmọ Lefi ni Jeṣua, Binnui, Kadmieli, Ṣerebiah, Juda àti Mattaniah ẹni tí òun pẹ̀lú àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀, ni wọn ṣe àkóso orin ìdúpẹ́.
9
Bakbukiah àti Unni, àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn dúró sí òdìkejì wọn nínú ìsìn.
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Options