Nehemiah 12:1-7
1
Àwọn wọ̀nyí ni àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi tí ó bá Serubbabeli ọmọ Ṣealitieli àti Jeṣua padà: Seraiah, Jeremiah, Esra,
2
Amariah, Malluki, Hattusi,
3
Ṣekaniah, Rehumu, Meremoti,
4
Iddo, Ginetoni, Abijah,
5
Mijamini, Moadiah, Bilgah,
6
Ṣemaiah, Joiaribu, Jedaiah,
7
Sallu, Amoki, Hilkiah, àti Jedaiah. Wọ̀nyí ni olórí àwọn àlùfáà àti àwọn ẹlẹgbẹ́ ẹ wọn ní ìgbà ayé e Jeṣua.
Settings