Skip to content
Luku 2:28-32

Luku 2:28-32

28
Nígbà náà ni Simeoni gbé e ní apá rẹ̀, ó fi ìbùkún fún Ọlọ́run, ó ní:
29
“Olúwa Olódùmarè, nígbà yìí ni ó tó jọ̀wọ́ ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ lọ́wọ́ lọ, ní àlàáfíà, gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ rẹ.
30
Nítorí tí ojú mi ti rí ìgbàlà rẹ ná,
31
tí ìwọ ti pèsè sílẹ̀ níwájú ènìyàn gbogbo;
32
ìmọ́lẹ̀ láti mọ́ sí àwọn aláìkọlà, àti ògo Israẹli ènìyàn rẹ̀.”
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Options